JayMikee – Talebale +[Video & Lyrics]
Talebale by JayMikee Mp3 Download
Download Nigerian gospel song from JayMikee titled Talebale. Popularly known as Jaymikee, Joshua Mike Bamiloye is the second son of Evangelist Mike and Gloria Bamiloye, drama evangelists, ministers and veteran actors of the Mount Zion Faith Ministries. Born on November 7, 1997, Joshua Mike Bamiloye has grown to become a music artiste, movie actor and evangelist.
Use this link below to stream and download track.
WATCH VIDEO
Lyrics Of Talebale by JayMikee
A jẹ’ bí ọmọdé tí ìyá rẹ rán lọ s’ọjà
Ah ah ah ah ah ah Ọjà ilé ayé láti ra láti tá Ah ah ah ah ah ah Ṣùgbọ’n tí ilẹ’ bá bẹ’rẹ’ si ní ń ṣú Tí òkùnkùn bá bo ‘lẹ’ Ti oníkálukú bá pá lẹ ọjà mọ Ma jẹ’ kí ń gbàgbé láti kọ ‘ri si ‘lèJésù ó jọ’wọ’ ó má má jẹ’ ń kùnà
Kíi má bá ṣ’ ègbé ló ṣe kú fún mi Jésù ó jọ’wọ’ ó má má jẹ’ n ṣìnà Kíi má bá ṣ’ ègbé ló ṣe kú fún mi Nígbà t’álẹ’ bá lẹ’ T’ọjà ayé tú Jẹ’ kí n r’ ọkọ rẹ bá relé Nígbà t’álẹ’ bá lẹ’ T’ọjà ayé tú Jẹ’ kí n r’ ọkọ rẹ bá reléÌjọba ọrùn dá bí àwọn wúńdíá mẹ’wàáTí wọn mú fìtílà wọn lọ pàdé ọkọ ìyàwó Ah ah ah ah ah ah ah Elédùmarè má má jẹ’ kí n dí alaigbagbọn Fún mi ní ọgbọ’n bí àwọn wúńdíá ọlọ’gbọ’n Kólóbó mì rèé ó Rọ’ kún pẹ’lú òróró rẹ Kíi n fí dúró dé ọ’
Ah ah ah ah ah ah ahJésù ó jọ’wọ’ ó má má jẹ’ ń kùnà
Kíi má bá ṣ’ ègbé ló ṣe kú fún mi Jésù ó jọ’wọ’ ó má má jẹ’ n ṣìnà Kíi má bá ṣ’ ègbé ló ṣe kú fún mi Nígbà t’álẹ’ bá lẹ’ T’ọjà ayé tú Jẹ’ kí n r’ ọkọ rẹ bá relé Nígbà t’álẹ’ bá lẹ’ T’ọjà ayé tú Jẹ’ kí n r’ ọkọ rẹ bá reléMú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé)
Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé (Bá relé) Mú Mí délé ó ó Mú mi délé Mú Mí délé ó ó Mú mi délé Mú Mí délé ó ó Mú mi délé Mú Mí délé ó ó Mú mi déléJésù ó jọ’wọ’ ó má má jẹ’ ń kùnà
Kíi má bá ṣ’ ègbé ló ṣe kú fún mi Bàbá jọ’wọ’ ó má má jẹ’ n ṣìnà Kíi má bá ṣ’ ègbé ló ṣe kú fún mi Nígbà t’álẹ’ bá lẹ’ T’ọjà ayé tú Jẹ’ kí n r’ ọkọ rẹ bá relé Nígbà t’álẹ’ bá lẹ’ T’ọjà ayé tú Jẹ’ kí n r’ ọkọ rẹ bá relé Baba Ah!